International News - A Yoruba Perspective

From BBC


Lónìí ni ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ kòtẹ́milọ́rùn tí PDP pe Gómìnà Dapo Abiodun yóò dájọ́
Oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Ladi Adebutu tako esi idibo gomina ipinlẹ Ogun, o si n sọ fun ileẹjọ lati kede oun gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu eto idibo naa.

Ohun tó wáyé níbi ìjókòó ìgbìmọ̀ olùwádìí lórí ikú Mohbad rèé
Igbimọ onigbẹjọ Korona wa sun ijoko siwaju di ọjọ kẹtala osu Kẹwa ọdun 2023 nigba ti awọn ẹlẹri ti wọn pe lori iku Mohbad yoo yọju sibẹ.

Bùọ̀dá àdúgbò ni Kamo jẹ́ sí mi, ọjọ́ tá a bẹ̀rẹ̀ àwàdà la ra àṣọ àti koto Nepa - Ozain
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ozain ni ko si ija kankan laarin oun ati Kamọ, awọn si maa n sọrọ daadaa.

Wọ́n fi ẹ̀sùn ìjówókó lọ sókè òkun kan ìyàwó ààrẹ Ali Bongo Gabon táwọn ológun gbàjọba rẹ̀
Olupẹjọ, Andre Patrick Roponat kede lọjọ Ẹti pe awọn ẹsun naa ti de iwaju adajọ bayii.

Ìbúgbàmù àdó olóró ṣekúpa èèyàn àádọ́ta níbi ayẹyẹ àjọ̀dún ọjọ́ ìbí ànọ́bì
Ni ibẹrẹ oṣu yi, o kere tan eeyan mọkanla to fi mọ gbajumọ olori awọn musulumi kan lo farapa ninu ibugbamu lagbegbe yio kanna.

Kí ni Uba Sani àti Isa Ashiru ń sọ nípa ìdájọ́ ìgbìmọ̀ tó ń gbẹ́jọ́ awuyewuye èsì ìdìbò Gómìnà ní Kaduna
Igun kọọkan ti ọrọ idajọ yi kan lo n sọ pe awọn lo jare pẹlu idajọ ti igbimọ to n gbẹjọ awuyewuye gbe kalẹ lỌjọbọ ni Kaduna.

Sọ́jà méjìlá kú ní Niger torí ìkọlù àwọn alákatakítí ẹ̀sìn
Minisita eto abo ilẹ naa lo fi ọrọ ọhun lede ninu atẹjade kan.

Ọmọ aṣofin kan l‘Oyo àti akẹ́kọ̀ọ́ LAUTECH márùn-ún pẹ̀lú awakọ̀ ló jóná nínu ìjàmbá mọ́tò
Agbẹnusọ fajọ FRSC, Agnes Ogungbemi, to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ sọ pe ere asapajude lo ṣokunfa rẹ.

Ìdúnkookò bẹ̀rẹ̀ láti yọ ààrẹ Amẹ́ríkà, Joe Biden nípò torí ẹ̀sùn tí wọn fi kan ọmọ rẹ̀
Ile ijọba ilẹ Amẹrika si ti sapejuwe igbesẹ iwadi aarẹ Biden yii gẹgẹ bii ‘ete oselu’ lasan.

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọ̀kan lára àwọn afurasí tó ṣekúpa DPO Bako
Ijọba ipinlẹ Rivers naa gbe ọgọrun ùn miliọnu silẹ fun ẹnikẹni to ba le ri ẹni to pa SP Bako Angbashim.

Ohun tó wáyé níbi ìjókòó ìgbìmọ̀ olùwádìí lórí ikú Mohbad rèé
Igbimọ onigbẹjọ Korona wa sun ijoko siwaju di ọjọ kẹtala osu Kẹwa ọdun 2023 nigba ti awọn ẹlẹri ti wọn pe lori iku Mohbad yoo yọju sibẹ.

Ìpè pàjáwìrì sí BBC dóòlà ẹ̀mí obìnrin mẹ́fà tó há sínú ọkọ̀ yìnyín
Fidio kan ṣafihan inu ọkọ akẹru ti ẹru kun inu rẹ, ati aye diẹ tàwọn to wa ninu rẹ jokoo sí.

Ṣé ríró òkú tàbí 'Autopsy' ló dára jùlọ láti tú àṣírí òkú tí wọn bá pa?
BBC Yoruba tọ awọn oniṣẹṣe lọ lati beere pe ki ni itumọ oku riro, bawo ni wọn ti n se e, awọn eroja wo ni wọn n lo ati ipa ti igbesẹ riro oku yii le ni lori mọlẹbi oku ati oku gan.

Sam Larry ti wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá
Agbẹnusọ ileeṣẹ naa, Benjamin Hundeyin lo fi ọrọ ọhun lede ninu atẹjade kan loju opo Twittter rẹ.

Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ LAUTECH jóná nínú ìjàmbá mọ́tò, àwọn aláṣẹ fásítì ní àwọn kò tíì lè sọ ìyè akẹ́kọ̀ọ́ tó ku
Agbẹnusọ fajọ FRSC, Agnes Ogungbemi, to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ sọ pe ere asapajude lo ṣokunfa rẹ.

Ìdí réè tàwọn ọdọ̀ kàn ṣe pé ìjọba orílẹ̀-èdè 32 lẹjọ̀ lórí ìyípadà ojú ọjọ́
Awọn olupẹjọ sọ pe igbesẹ ijọba lati ma ya si ọrọ iyipada ayika jẹ itapa si ẹtọmọniyan awọn.

Bí ajá bá bù yín jẹ aporó kò ràn án, abẹ́rẹ́ àìsàn dìgbòlugi lòògùn rẹ̀ -Oníṣègùn
Lọpọ igba lawọn eeyan a maa fi ọwọ yẹpẹrẹ mu u ti aja ba bu wọn jẹ lae mọ pe kokoro digbolugi le ti wọ inu ara wọn.

Ìyàwó fi ọmọ-odó lu ọkọ rẹ̀ pa l'Ondo, ló bá f'ẹsẹ̀ fẹ
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Arabinrin Funmilayo Odunlami to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ ni awọn agbofinro ti bẹrẹ iṣẹ lati wa obinrin naa ri ki o le foju wina ofin.

Sọ́jà méjìlá kú ní Niger torí ìkọlù àwọn alákatakítí ẹ̀sìn
Minisita eto abo ilẹ naa lo fi ọrọ ọhun lede ninu atẹjade kan.

Obasanjo tàbùkù àwọn Ọba Yorùbá, ó gbọdọ̀ tọrọ àforíjìn - Afenifere
Ninu atẹjade to fi sita lẹyin ipade rẹ ni Ọjọru niluu Akure, Afenifere sọ pe Obasanjo gbọdọ tọrọ aforijin lọwọ awọn Ori-ade tọrọ kan.

Ète ìdìtẹ̀gbàjọba wáyé ní Burkina Faso, ọwọ́ tẹ àwọn ológun tó fẹ́ dìtẹ̀gbàjọba
Diẹ lo ku ko pe ọdun kan bayii ti awọn ologun naa gbajọba, ti ọgagun Ibrahim Traoré si sọ ara rẹ di Aarẹ fidihẹ orilẹ-ede naa.

Kí ni Autopsy? Báwo la ti ń ṣe é, ọjọ́ mélòó ni èsì rẹ̀ máa ń jáde?
Ìwádìí òkú Mohbad ń wáyé lẹ́yìn tí àwọn ọmọ Nàìjíríà dìde pé ó yẹ kí wọ́n ṣe àyẹ̀wò òkú náà láti fìdí ohun tó ṣekúpa olórin náà múlẹ̀.

Ọ̀pọ̀ ajínigbé ya bo abúlé Alálùbọ́ṣà ní Kwara, ẹ̀mí bọ́, ọ̀pọ̀ farapa
Alukoro ọlọpaa nipinlẹ Kwara, Ajayi Ọkasanmi, sọ fun BBC Yoruba bi isẹlẹ naa se waye ati bi igbesẹ ti wọn gbe lori rẹ.

Azerbaijan gba àkóso agbègbè Nagorno-Karabakh, ìró ìbọn ń dún lákọlákọ, ọ̀pọ̀ èèyàn sá àsálà fún ẹ̀mí wọn
Kaakiri agbaye ni igbagbọ ti wa pe ara ile Azerbaijan ni Nagorno-Karabakh wa, amọ lati nnkan bii ọgbọn ọdun sẹyin ni ilẹ naa ti wa ikawọ ijọba Armenia, ti awọn eeyan to n gbe ibẹ si n padanu ẹmi wọn lọwọ oniruru ija to naa ma waye nibẹ.

Láéláé, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò ní yanṣẹ́ lódì, ìkéde ayọ̀ ń bọ̀ lọ́jọ́ òmìnira - Tinubu
Ọjọ Kẹta oṣu kẹwaa ni awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ sọ pe iyanṣẹlodi ọlọjọgbọọrọ yi yoo bẹrẹ jakejado Naijiira.

Wo ibùdó ìgbafẹ́ pàtàkí nílẹ̀ Yorùbá to le pa owo gọbọi wọle fáwọn ìpínlẹ̀ tí wọn wà
Lọna ati sami ayajọ ọjọ irinajo afẹ l'agbaye yii, lo mu ki BBC Yoruba ṣe akojọpọ ọkanojọkan ibudo afẹ ti o lagbara lati pa owo gọbọi wọle fun ijọba nilẹ Yoruba.

"Ohun tó wù mí jùlọ ni kí n ṣí ara àti orí sílẹ̀ àmọ́ wọ́n kan Hijab nípá fún mi láti wọ̀"
Obinrin musulumi mẹta sọ iriri wọn fun BBC nipa yiyọ Hijab lórí, bi o tilẹ jẹ pe wọn n koju atako to lagbara.

Wo ìgbésẹ̀ pàjáwìrì méje fún ìdóòlà ẹ̀mí fún ẹní tó n pọ̀kàkà ikú
Njẹ ẹ mọ awọn igbesẹ idoola ti ẹ le sare gbe ti eeyan ba wa ninu ewu tabi to n pọkaka iku? Alaye ree.

Ìdí rèé tí àwọn ènìyaǹ kan kò fi gbàgbọ́ nínú kòkòrò àìfojúrí
Ìwádìí fi hàn pé àwọn tó kó ara wọn jọ, tí wọn kò gbàgbọ́ nínú agbára kòkòrò àìfojúrí yìí bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn ọdún 2020 láti ìgbà tí àìsàn Covid-19 ti wáyé.

Ìjọba Oyo kò ní gbára lé owó láti òkè mọ́, á dojú kọ owó lára ìrìnàjò afẹ́ - Olatunbosun
Ọmọwe Wasiu Olatunbosun lo fi idi eyi mulẹ nibi ayẹyẹ ipatẹ lati sami ayajọ irinajo afẹ lagbaye to waye ninu Gbongan Bowers Tower nilu Ibadan.

Ọkọ, ìyàwó ọ̀sìngín àti èèyàn 113 míì jóná di eérú, 150 farapa níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó
Igbakeji gomina Nineveh, Hassan al-Allaq, ti sọ fun ileeṣe iroyin Reuters pe apapọ eeyan mẹtalelaadọfa (113) lo ba iṣẹlẹ ọhun lọ.

Olórí ẹgbẹ́ awakọ̀èrò l’ Eko, MC Oluomo ránṣẹ́ ìkìlọ̀ sí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC
Wahala bẹ silẹ laarin awọn igun to n naga lati de ori ipo aarẹ ẹgbẹ awakọ ero NURTW lorilẹede Naijiria,

Wo ẹ̀sùn mẹ́rìnlá tí ilé aṣòfin Ondo fẹ́ fi yọ igbákejì gómìnà, Aiyedatiwa nípò
Oriṣiriṣi ẹgbẹ lo ti bẹrẹ iwọde ifẹhonuhan ni ilu Akure tako igbesẹ yiyọ igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Lucky Aiyedatiwa.

Ẹ sinmi agbaja, ẹbí Mohbad ló ní ẹ̀tọ́ láti ṣàyẹ̀wò DNA fún ọmọ rẹ̀ - Iyabo Ojo
Ẹ ó rántí pé láti ìgbà tí olórin tàkasúfèé náà, Mohbad jáde láyé lọ́jọ́ Kejìlá oṣù Kẹsàn-án ọdún 2023 ni àwọn ọmọ Nàìjíríà ti ń pè fún ìwádìí lórí ikú rẹ̀.

Mohbad kò bá má kú, ká ní òun àtàwọn òbí rẹ̀ sá di OPC tàbí sọ fún wa nípa ìdojúkọ rẹ̀ – OPC
Ọjọ Kejila oṣù kẹsàn-án ọdun 2023 ni ariwo ta pe gbajumọ akọrin takasufe kan, Ilerioluwa Aloba, ti ọpọ eeyan mọ si Mohbad, ku lasiko aisan ranpẹ.

Ojú lásán kọ́ ni ọ̀rọ̀ iná tó jó ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ, ejò lọ́wọ́ nínú – PDP yarí
Atẹjade kan ti agbẹnusọ ẹgbẹ oselu PDP, Debo Ologunagba, fi lede lo ti kede pe ejo lọwọ ninu ijamba ina to waye nile ẹjọ to ga julọ.

Kí ló ń fa gbas-gbos láàrín Olowo ìlú Owo àti Ojomo Oluda Ijebu-Owo lásìkò ọdún Igogo?
Ọdun igogo ti wọn bẹrẹ rẹ ni ẹgbẹta ọdun o le diẹ sẹyin, ni wọn n ṣe ni iranti ayaba kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Ọ̀rọnṣẹ̀n.

HUMILITASCharleans' Contribution Worldwide

300

Charlean Doctors

250

Charlean Engineers

150

Charlean Lawyers

109

Charlean Professors

We always perform at our best when we work together

Our mission is to provide the means & technical know-how to accomplish the aforementioned with HUMILITAS - always