International News - A Yoruba Perspective

From BBC


Wo ìrànlọ́wọ́ tó yẹ kí o ṣe fún ẹni tí rọpárọsẹ̀ bá kọlù lójijì
Bo ti wu ko kere to, akoko diẹ ti eeyan ba fi ṣofo ko too bẹrẹ itọju rọparọsẹ le di isọro nla, o si le fa iku ẹni ti aisan naa kọlu.

Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà dá Fred Ajudua padà sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn jìbìtì $1.43m
Ẹ ó rántí pé ni ilé iṣẹ́ Palestine, nínú lẹ́tà kan tí wọ́n kọ lọ́jọ́ Kẹrìndínlọ́gbọ̀n, oṣù Kẹjọ, ọdún 1993 sí Mínísítà fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè àti ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìgbà náà ni wọ́n ti fẹ̀sùn kan Ajudua pé ó fi ọ̀nà èrú gba owó $1.43m lọ́wọ́ Ziad Abu Zalaf, ọmọ orílẹ̀ èdè Palestine tó ń gbé ní Germany.

Àlàyé rèé lórí ìbáṣepọ̀ tó wà láàrin ọpọlọ àti ikùn ẹ̀dá
Awọn onimọ sọ pe ile aye miran ni inu ikun ẹda.

Ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìrìnàjò mímọ́ sí Saudi Arabia lọ̀dún yìí
Irinajo Hajj jẹ ọkan pataki lara awọn opo ẹsin Islam, paapaa fun ẹni to ba lagbara lati rinrinajo naa.

Ọkùnrin tí Salawa ń fẹ́ báyìí ń yá a lò ni, ìyàwó mi ni títí ayé - Kollington Ayinla
Lori eto kan, 'Tejubabyface show', ni Kollington ti sọ laipẹ yii nipa Salawa, pe iyawo oun ni titi aye.

Bàbá Mohbad le pe ẹjọ́ tako ìdájọ́ tó tú Naira Marley àti Sam Larry sílẹ̀ - Ilé ẹjọ́
Baba Mohbad ní igbẹjọ to tu Naira Marley ati Sam Larry silẹ ko fun gbogbo awọn ti ọrọ naa kan lanfani lati wa sọ tẹnu wọn.

Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ iṣẹ́ ọnà jẹ́wọ́ ẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí lẹ́yìn tó tajà fún 'agbódegbà Hezbollah'
Wọn fi to ile ẹjọ leti lọjọ Ẹti pe Ojiri ta iṣẹ ọna ti owo rẹ to £140,000) fun Nazeem Ahmad, ẹni ti wọn n fi ẹsun kan pe o n ṣe agbatẹru ẹgbẹ agbesunmọmi Hezbollah.

Mọ̀ nípa Joan, obìnrin tó ṣe bí ọkùnrin tó fi di Póòpù ìjọ Àgùdà
Póòpù Joan ni ìgbàgbọ́ wà pé ó ṣe póòpù fún ọdún bíi méjì, ìtàn yìí gbajúmọ̀ àmọ́ tó tún fa ọ̀pọ̀lọpọ̀ awuyewuye lásìkò tó ṣẹlẹ̀.

Tito Harrison, gbajúmọ̀ òṣèré tíátà ṣàlàyé àìsàn tó sọ ọ́ di aláìní, tó ṣe ń gbé ilé àna rẹ̀
Ṣadeede ni awọn eeyan ko gbọ nnkan kan nipa Tito Harrison mọ, ko si ninu awọn iṣẹ to n jade mọ, bẹẹ ni iroyin ko sọ nipa rẹ.

Kí nídìí tí Póòpù tuntun fi yan Leo XIV gẹ́gẹ́ bí orúkọ oyè rẹ̀ tuntun?
Iṣẹ́ àkọ́kọ́ tí póòpù tuntun máa ń ṣe ni pípàrọ̀ orúkọ tí wọ́n sọ ọ́ sí orúkọ tuntun.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Wo bí àwọn obìnrin ṣe ń rí ikú he láti ọwọ́ àwọn ọkùnrin ní Naijiria
Lara iku awọn obinrin to ti ọwọ ọkunrin ti wọn pe ni ololufẹ waye, ni ti ọmọbinrin kan, Onuwabuagbe Augusta Osedion, ẹni ọdun mọkanlelogun ( 21).

Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ fún Gómìnà Adeleke ní gbèdéke ọjọ́ láti yanjú owó ilé tó ń fò lókè l'Osun
Agbẹnusọ naa sọ pe o ṣe ni laanu pe ijọba ko ṣe ohunkohun si ọrọ yii latilẹ, to fi di pe awọn onile n gbe owo rẹpẹtẹ le ile wọn.

"Mò ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní ìmọ̀ ẹ̀kọ́ Kẹ́mísírì lédè Yorùbá, fún àgbéga akẹ́kọ̀ọ́ àti èdé abínibí"
BBC Yorùbá bá olùkọ́ kan tó ń fi èdè Yorùbá kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sọ̀rọ̀, ó sì ṣàlàyé ohun tó sun dé ìdí ìgbésẹ̀ náà.

Ọ̀ná là ní ẹnu ibodè Seme àti Badagry bí Tinubu ṣe fagilé ìgbégidínà lójú ọ̀nà Nàíjíríà sí ilẹ̀ Benin
Aṣoju Musa Nuhu, aṣoju Naijiria fun ECOWAS lo kede eyi lasiko abẹwo rẹ si ẹnubode orilẹede Naijiria ati ilẹ Benin ni Seme.

Ariwo sọ bí ọ̀dọ́bìnrin kan ṣe parọ́ pé wọ́n jí òun gbé lásìkò tó wà pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀, ọlọ́pàà sọ̀rọ̀
Agbẹnusọ ọlọpaa Ekiti, Sunday Abutu, lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin.

Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Robert Prevost Leo XIV, Póòpù tuntun fún ìjọ Kátólíìkì
Robert Prevost ni Popu akọkọ lati orilẹede Amẹrika, bi o tilẹ jẹ wi pe ọpọlọpọ eeyan lo tun n fi oju ara ilẹ Larin Amerika wo o.

"Kí àlááfíà wà pẹ̀lú yín" Pope tuntun, Leo XIV bá àgbáyé sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́
Lọjọbọ ni wọn kede orukọ Robert Prevost gẹgẹ niẹni ti yoo maa dari ijọ naa lẹyin ipapoda Popoe Francis.

Kí ni ìdí tí India àti Pakistan fi ń jà sí agbègbè Kashmir?
Ṣaaju ki India ati Pakistan to gba ominira wọn lọwọ ijọba ilẹ Gẹẹsi, ni wọn ti n ja si agbegbe Kashmir yii.

Joe Biden korò ojú pé Donald Trump ń sọ̀rọ̀ ṣàkàṣàkà, kò sọ̀rọ̀ bíi Ààrẹ Amẹ́ríkà
Aarẹ Amẹrika ana naa sọrọ lori erongba rẹ nipa Aarẹ Donald Trump to wa lori alefa lọwọ.

"Lẹ́yìn tí Ajínigbé gba N14m owó ìtúsílẹ̀, àpò ìrẹsì, adìẹ méjìlá tí wọn dín gbẹ, ohun mímu 24, káàdì ìpè N10,000, wọ́n tún ń bèèrè N70m míì"
BBC Yorùbá kàn sí méjì nínú àwọn ẹbí àwọn èèyàn méje tí wọn jí gbé náà, tí wọn sì ṣàlàyé bí aáyan wọn láti gba ìdásílẹ̀ àwọn èèyàn wọn lọ́wọ́ ajínigbéc, ṣe já sí pàbó.

Ètò yíyan Póòpù tuntun ń tẹ̀síwájú bí èéfí dúdú ṣe jáde láti Sistine Chapel
Èéfín dúdú ló jáde lálẹ́ àná ní Sinistine Chapel tí ètò ìdìbò náà ti ń wáyé, tí èyí sì túmọ̀ sí pé àwọn cardinal náà kò ì fẹnukò lórí ẹni tó máa di póòpù tuntun.

Àlàyé rèé lórí ìdí tí aáwọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú Labour ṣe ń le koko sí, bí igun Abure àti Usman se dojú ogun kọ ara wọn
Ikọ̀ ti Usman, tí Alex Otti àti Peter Obi faramọ́, ti fún Abure ní ọjọ́ méjì láti yé pe ara rẹ̀ ní alága ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Party mọ́ nítorí sáà rẹ̀ ti parí.

Fídíò rèé nípa bí wọn ṣe máa ń yan Póòpù tuntun
Ipade ti wọn maa n ṣe lati yan olori ijọ Aguda tuntun naa lo n waye lẹyin isin Novemdiales, eyi ti wọn ṣe lati tọrọ isinmi ayeraye fun Poopu Francis to di oloogbe.

Ìdí rèé tí Bàálù Herbert Wigwe fi já ní Amẹ́ríkà èyí tó rán òun, aya àti ọmọ rẹ̀ sọ́run lójijì
Abajade nipa ohun to fa a ti baalu to gbe Herbert Wigwe ati ẹbi rẹ fi ja, lo wa ninu atẹjade abọ iwadii ti ajọ to n se akoso eto irina ni Amẹrika gbe jade.

Ṣé lóòótọ́ ni Nnamdi Kanu pàṣẹ kí wọn máà pa àwọn ọlọ́pàá, tún lérí láti kọlu ìpínlẹ̀ Eko?
Ẹlẹrii yii jẹ oṣiṣẹ DSS. Ọkunrin naa fi awọn ẹri to n kede ibi ti Kanu ti n fun awọn kan laṣẹ lati ba Naijiria ja, han.

Ìyàwó gun ọkọ lọ́bẹ pa lẹ̀yìn ọjọ́ kẹsàn-án ìgbeyàwó
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Kano, SP Abdullahi Haruna Kiyawa ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Faraw ni ijọba Tarauni nipinlẹ Kano.

Wo ìgbésẹ̀ tí o le è gbé láti mọ̀ bóyá ojúlówó ni nọ̀ńbà NIN rẹ àti ànfàní lílo rẹ̀
Agbẹnus fun ajọ NIMC ni idasilẹ oju opo NIN Auth yoo pese aabo fun awọn iroyin nipa araalu, ti ọpọ ẹka ijọba yoo si jẹ anfani rẹ.

Àlàyé rèé lórí ìdí tí Póòpù fi máa ń wọ bàtà pupa àti ìdáhùn àwọn ìbéèrè míràn tó rú ọ lójú
Ọpọ eeyan lo ti n foju sọna si ibo ni agbaye ti Pope tuntun yoo ti wa.

Ìdí rèé tí mo ṣe lọ sọ́dọ̀ àjọ EFCC - Iyabo Ojo
Iyabo Ojo salaye pe ilẹ Gẹẹsi loun wa, ti EFCC fi ke si oun amọ ọjọ karun un, oṣu Karun un yii gan ni oun to yọju si EFCC nigba ti oun pada de si Naijiria.

Kí ló ń jẹ́ "Shadow Government", tí Pat Utomi gbé kalẹ̀ láti tako ìjọba Tinubu?
Pat Utomi sọ pé àwọn ṣàgbékalẹ̀ ìjọba òdìkejì náà tó pe orúkọ rẹ̀ ní "Big Tent Coalition Shadow Government" lórí ayélujára.

Ètò yíyan Póòpù tuntun ń tẹ̀síwájú bí èéfí dúdú ṣe jáde láti Sistine Chapel
Èéfín dúdú ló jáde lálẹ́ àná ní Sinistine Chapel tí ètò ìdìbò náà ti ń wáyé, tí èyí sì túmọ̀ sí pé àwọn cardinal náà kò ì fẹnukò lórí ẹni tó máa di póòpù tuntun.

Bí ìgbẹ́jọ́ Alfa Abdulrahman tí wọn fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ àti ikú Afsot Yetunde kàn ní Ilorin ṣe lọ lónìí rèé, bí bàbá olóògbé ṣe bú sẹ́kún
Awọn olujẹjọ maraarun ti wọn fi ẹsun ipaniyan naa kan, to fi mọ Alfa Abdulrahman, ni wọn farahan ni ile ẹjọ naa.

Boko Haram ti gboró, bàálù Drone ló ń lò láti kọlu aráàlú ní Borno - Aṣojú-ṣòfin
Jaha ni awọn ohun ija to wa lọwọ awọn agbebọn Boko Haram ju eyi to wa lọwọ awọn ọmọ Ologun Naijiria lọ.

UK gbé ìlànà tuntun kalẹ̀ lórí 'Visa' gbígbà ní Nàìjíríà àti orílẹ̀èdè méjì míì
Lábẹ́ ìlànà Home Office tuntun yìí, èyí tí Times kọ́kọ́ gbé jáde, àwọn èèyàn láti Pakistan, Nigeria àti Sri Lanka ni ó ṣéeṣe kó ṣòro láti rí físà wọ UK tún le díẹ̀ si.

HUMILITASCharleans' Contribution Worldwide

300

Charlean Doctors

250

Charlean Engineers

150

Charlean Lawyers

109

Charlean Professors

We always perform at our best when we work together

Our mission is to provide the means & technical know-how to accomplish the aforementioned with HUMILITAS - always