International News - A Yoruba Perspective

From BBC


Ètò ìdìbò abẹ́lé APC Ondo yóò wáyé lónìí, wo àwọn olùdíje sí ipò Gómìnà
Eyi ni awọn koko ọrọ to yẹ ko mọ nipa awọn oludije to gbe igba idibo naa

Ọwọ́ tẹ ọmọ ọdún mẹrìnlélógún tó jí ara rẹ̀ gbé ní Kwara
Ọga ọlọpaa nipinlẹ naa, Victor Ọlaiya lo ṣalaye ọrọ yii lẹkunrẹrẹ fawọn akọroyin niluu Ilọrin lasiko to n ṣafihan Afọlabi lori iwa ọdaran to hu.

Mo kọ́kọ́ rò pé kò dáa kí onígbàgbọ̀ wá olólùfẹ́ lórí ayélujára 'Dating APP'
Oni Opeyemi ati Ogunlaja Temitope ba BBC Yoruba sọrọ lori irinajo ifẹ wọn ati bi wọn ṣe pada loju opo ayelujara ati iha ti wọn kọ si wiwa ololufẹ lọ ayelujara.

Báwo ni ohun ìjà olóró Iran ṣe lágbára tó sí ti Israel?
Ajọ International Institute for Strategic Studies (IISS) ṣapejuwe agbara awọn ohun ija oloro ileeṣẹ ologun orileede mejeeji yii nipa lilo ọrọ awọn agbẹnusọ, ati awọn miran to ṣee tọka si lati fi gbe abajade wọn sita.

Mọ̀ nípa Tunde Onakoya tó fi ìtàn GWR balẹ̀ lórí eré Chess
Mílíọ̀nù kan dọ́là ni Onakoya ń gbìyànjú láti kó jọ láti fi ṣàtìlẹyìn fún ẹ̀kọ́ chess káàkiri àgbàyé.

Ọ̀gá ọlọ́pàá pàṣẹ kí àwọn ẹ̀sọ́ ààbò tó wà lẹ́yin Yahaya Bello kúrò
Ọga ọlọpaa lo kede pe ki awọn ọlọpaa to n ṣọ gomina ana naa kuro lẹyin rẹ ninu atẹjade ti nọmba rẹ jẹ CB:4001/DOPS/PMF/FHQ/ABJ/VOL.48/34, eyi ti ileeṣẹ ọlọpaa gbe jade laarọ oni, ọjọ Ẹti, gẹgẹ bi iwe iroyin PUNCH ṣe kọ ọ.

Ooni sọ̀rọ̀ lórí bí ó ṣé ń ṣé ètò ìlú pẹ̀lú ètò àwọn ayaba l'ààfin
Nigba to n ba BBC News Yoruba sórọ, Ooni ni Ọlọrun Olodumare atawọn Alaṣeku lo n ba oun ṣe ti ikankan ko fi di ara wọn lọwọ.

Israel ju àdó olóró sí àárín gbùngbùn Iran, ariwo sọ
Iran la gbọ pe wọn ti gbaradi gidi nigba ti awọn Israel sọ pe awọn yoo gbẹsan ikọlu ti awọn ara Iran ṣe si wọn lọjọ Abamẹta to kọja.

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 46 tó ń da omi àlááfíà Ilorin rú
Awọn afurasi ọhun tun ṣa onikẹkẹ maruwa kan Abdullahi Alao, pa.

Ẹnikẹ́ni tó bá dènà àwọn òṣìṣẹ́ wa lọ́wọ́ láti ṣiṣẹ́ wọn yóò fi ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún gbára – EFCC
Nínú àtẹ̀jáde kan tí EFCC fi sórí FACEBOOK wọn lọ́jọ́bọ̀ ni wọ́n kéde àwọn ń wá Yahaya Bello lórí ẹ̀sùn tó ní ṣe pẹ̀lú kíkó owó ìlú tó lé ní ọgọ́rin bílíọ̀nù náírà jẹ.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo da ibùba àwọn ajìjàgbara Oodua Nation wò nílùú Ibadan
Bẹẹ ba gbagbe, awọn ikọ ajijagbara Oodua Nation yii lo kọlu ọgba ọfisi gomina ipinlẹ Oyo ati ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo ti wọn gbero lati gba ijọba

Wọ́n ní wọ́n ti ń mú ‘kinní’áwọn ọkùnrin Ghana mọ́ wọn lára láàrin ọjá áti ígboro
Ẹ o ranti pe iroyin nnkan ọmọkunrin pipoora yii ti gbode kan lorilẹ-ede Naijiria naa ri, ko too dohun to lọ sokun igbagbe bayii.

Ẹnikẹ́ni tó bá dènà àwọn òṣìṣẹ́ wa lọ́wọ́ láti ṣiṣẹ́ wọn yóò fi ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún gbára – EFCC
Nínú àtẹ̀jáde kan tí EFCC fi sórí FACEBOOK wọn lọ́jọ́bọ̀ ni wọ́n kéde àwọn ń wá Yahaya Bello lórí ẹ̀sùn tó ní ṣe pẹ̀lú kíkó owó ìlú tó lé ní ọgọ́rin bílíọ̀nù náírà jẹ.

A máa pinnu bí ìkọlù sí Iran padà yóò ṣe wáyé - Israel sọ fún UK
Netanyahu ní ìjọba òun yóò ṣe gbogbo òun tó wà ní ìkáwọ́ òun láti dá ààbò bo orílẹ̀ èdè Isreal.

Ọwọ́ ba Gbadebọ tí wọ́n ló lu èèyàn pa níbi ìsìnkú bàbá rẹ̀
Odutọla fidi ẹ mulẹ, pe ẹka to n tọpinpin iwa ọdaran lawọn yoo taari afurasi yii si.

Chris Oyakhilome: Pásítọ̀ Nàíjíríà tó n bu ẹnu àtẹ́ lu abẹ́rẹ́ àjẹsára tó n dèna àìsàn ibá
Ọyakhilome wa lara awọn pasitọ ti ko gbagbọ ninu lilo oogun oyinbo tabi ti ibilẹ, ṣugbọn to gbagbọ daadaa ninu iṣẹ iyanu ati iwosan atokewa, eyi ti awọn oloyinbo n pe ni ‘Miracle and Divine Healing’.

A ṣe àṣìṣe, kìí ṣe DJ Switch ni a mú - Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá
Ṣe lootọ ni pe Ileeṣẹ Ọlọpaa ti mu gbajugbaja oluwọde Endsars, Obianuju Catherine Udeh ti ọpọ mọ si DJ Switch saa ahamọ?

Ọmọ ogun ṣekúpa obìnrin kan, gbé òkú rẹ̀ pamọ́ ní bárékè- Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ológun náà, Nwachukwu bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìṣẹ̀lẹ̀ náà banilọ́kàn jẹ́ nítorí ẹ̀mí èèyàn bá a lọ, ó ní ohun ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé àwọn kan ń gbe kiri pé ọmọ ikọ̀ Boko Haram tó ti sọwọ́lẹ̀ fún ìjọba ló ṣe ìkọlù náà.

Ilé ẹjọ́ buwọ́lu ìyọ̀nípò Ganduje, ariwo sọ
Ẹsun siṣe owo ilu mọkumọku ni wọn fikan Ganduje

Ètò ìdìbò abẹ́lé APC Ondo yóò wáyé lónìí, wo àwọn olùdíje sí ipò Gómìnà
Eyi ni awọn koko ọrọ to yẹ ko mọ nipa awọn oludije to gbe igba idibo naa

Bíṣọ́ọ̀bù tí wọ́n gún lọ́bẹ lóun ti dáríji àwọn tó kọlu oun
Ileeṣẹ ọlọpaa to fidi ikọlu ọhun mulẹ fawọn akọroyin sọ pe awọn agbebọn lo ṣe ikọlu naa, ti wọn si ṣe ọpọ awọn olujọsin, to fi mọ awọn olori ijọ leṣe.

Kò rọrùn, mo bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣé Másà ní ẹ̀yìnkùlé ilé Baba mi -Aisha Abimbola
O ni nitori pe oun fẹ da yatọ ninu awọn olopo yooku to n ṣe ounjẹ bi tiẹ ni oun fi yan siṣe Massa laayo gẹgẹ bii iṣẹ.

Adájọ́ faraya, ní òun le sún ìgbẹ́jọ́ Nnamdi Kanu láì ní gbèdéke ọjọ́ nítorí...
Ẹsun meje ọtọtọ to da lori idunkooko ati idaluru ni Kanu to n beere ijọba Biafra fawọn ẹya Igbo n jẹjọ rẹ bayii.

Wo ipa tí àdínkù owó lítà kan epo 'diesel' tí Dangote ṣe sí N1,000 yóò ní lórí aráàlú
Ni bi ọsẹ mẹta to kọja ni ile ifọpo rọbi Dangote kọkọ ṣe adinku owo epo disu lati N1,600 si N1,200.

Kóótù gba onídùúró Cubana Chief Priest pẹ̀lú mílíọnù mẹ́wàá náírà
Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ni ile-ẹjọ giga apapọ ju Bobrisky sẹwọn oṣu mẹfa gbako pẹlu iṣẹ aṣekara lai fi aye silẹ fun owo itanran rara.

Ọdún ọmọ ìlú Ìbarà bẹ̀rẹ̀ l’Abẹ́òkúta lákọ̀tun
Ẹẹkan ṣoṣo laarin ọdun mẹta ni ayẹyẹ Ọdun ọmọ Ibara maa n waye, nibi ti wọn ti maa n ṣafihan awọn ohun iṣẹmbaye wọn bii Yemọja, Ẹfẹ ati Gẹlẹdẹ, gẹgẹ bi a ṣe gbọ.

Israel ju àdó olóró sí àárín gbùngbùn Iran, ariwo sọ
Iran la gbọ pe wọn ti gbaradi gidi nigba ti awọn Israel sọ pe awọn yoo gbẹsan ikọlu ti awọn ara Iran ṣe si wọn lọjọ Abamẹta to kọja.

Sẹnetọ Rafiu Adebayọ jáde láyé lẹ́ni ọdún 57
Ọkunrin naa ni wọn lo ku lẹyin aisan rampẹ to kọlu, ti wọn si lo ti gba itọju, ṣugbọn ti ẹlẹmin tun pada gba a.

Àwọn agbébọn yawọ abúlé, jí àwọn obìnrin àti àwọn ọmọ gbe ní Katsina
Iṣẹlẹ yii ti sọ ọpọ awọn to n gbe lagbegbe naa di alainile lori ati ẹru awọn ajinigbe.

Bíṣọ́ọ̀bù tí wọ́n gún lọ́bẹ lóun ti dáríji àwọn tó kọlu oun
Ileeṣẹ ọlọpaa to fidi ikọlu ọhun mulẹ fawọn akọroyin sọ pe awọn agbebọn lo ṣe ikọlu naa, ti wọn si ṣe ọpọ awọn olujọsin, to fi mọ awọn olori ijọ leṣe.

'Orí ló kó mi yọ lọ́wọ́ ikú, àwọn ọ̀rẹ́ mi mẹ́rin ni wọ́n pa'
Ó ní ohun ìyàlẹ́nu ló jẹ́ fún òun pé òun móríbọ́ àti pé òun kàn farapa níbi èjìkà lásán ni.

Ọ̀rọ̀ epo pupa dá wáhàlá láàrin ìyá àti ọmọ rẹ̀ l'Osun, ẹ̀mí ìyá bọ́ síi
Nigba to fi idi iṣẹlẹ naa fun BBC News Yoruba, agbenusọ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola ni iwadii ti bẹrẹ lati mọ ohun to ṣokunfa aawọ naa.

Ilé ẹjọ́ buwọ́lu ìyọ̀nípò Ganduje, ariwo sọ
Ẹsun siṣe owo ilu mọkumọku ni wọn fikan Ganduje

A máa ṣe ìkọlù sí Iran padà – Israel fèsì
Netanyahu sọ pe awọn eeyan Isrẹli gan-an ti n dira ogun lati awọn ọdun diẹ sẹyin. Koda, ni gbogbo ọsẹ meloo sẹyin pẹlu ni wọn fojoojumọ mura silẹ de ogun ti Iran le gbe ko wọn.

Ààrẹ Bọla Tinubu kéde ọjọ́ keje, oṣù kẹrin ọdún gẹ́gẹ́ bí àyájọ́ ọjọ́ àwọn ọlọ́pàá
Igbakeji Aarẹ, Kashim Shettima to ṣoju Aarẹ Tinubu sọ pe latigba toun ti gba ijọba lọdun 2023 ni iṣakoso oun ti bẹrẹ igbesẹ lori atunto ninu iṣẹ ọlọpaa.

Kí ni òfin sọ nípa títàbùkù owó Náírà?
Gẹgẹ ọkan lara awọn alabojuto ọgba ẹwọn ti Bobrisky wa ṣe ṣalaye fun iwe iroyin PUNCH, wọn ni itọju to tọ si awọn ẹlẹwọn naa ni ọdọkunrin ọhun n gba lọgba ẹwọn awọn ọkunrin to wa.

Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 46 tó ń da omi àlááfíà Ilorin rú
Awọn afurasi ọhun tun ṣa onikẹkẹ maruwa kan Abdullahi Alao, pa.

A o kábamọ̀ ìgbésẹ̀ wá rárá - Afurasí ajìjàgbara Oodua Nation
Ninu atẹjade ileeṣẹ ọlọpaa Ọyọ ni wọn ti sọ pe iwa ọdaran gbaa to lodi sofin lawọn eeyan naa hu.

Lẹ́yìn ọdún kan tí ìja Sudan bẹ̀rẹ̀
Awọn araalu ti wọn ku, ọpọ wọn lo jẹ pe ọta ibọn lo ba wọn, lẹyin ti wọn ti gba ijọba papọ ninu iditẹ gbajọba ti ọdun 2021.

HUMILITASCharleans' Contribution Worldwide

300

Charlean Doctors

250

Charlean Engineers

150

Charlean Lawyers

109

Charlean Professors

We always perform at our best when we work together

Our mission is to provide the means & technical know-how to accomplish the aforementioned with HUMILITAS - always