It is within us to build this fraternity network so that others can see how we have utilised all that wonderful upbringing and so much more inculcated at St.Charles
Alaafin Owoade to gba ade Sango ni Koso lọjọ Abamẹta ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Kẹta niluu Oyo sọrọ yii ninu ọrọ ikini ku ọdun to fi ranṣẹ sawọn musulumi to n ṣe ọdun itunu awẹ.
Fidio ija Olanrewaju ati Mbanugu ti a ri lori itakun ayelujara fi idi rẹ mulẹ wi pe oun gan an lo n lewaju pẹlu ami ayo to pọju ninu ija ọhun ki o to ṣubu lulẹ.
Ọ̀pọ̀ àwọn tí ilẹ̀ rírì ṣàkóbá fún ni kò rí ọ̀nà láti àwọn ohun èlò ìrànwọ́ tí wọ́n pèsè fún wọn bí ilẹ̀ rírì náà ṣe ti ba ọ̀pọ̀ ọ̀nà àti ohun améyédẹrùn jẹ́.
Àtẹ̀jáde kan tí àjọ náà fi sórí ìkànnì ayélujára wọn lọ́jọ́ Ẹtì, ọjọ́ Kejìdínlọ́gbọ̀n, oṣù Kẹta ni wọ́n ti kéde pé àwọn ń wá obìnrin náà fẹ́sùn lílẹ̀dí àpòpọ̀ láti hùwà ọ̀daràn àti kíkó owó ìlú lọ sí ilẹ̀ òkèrè.
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́, wọ́n ní àwọn èèyàn tí wọ́n pa ọ̀hún ń ṣe ìrìnàjò lọ ní òpópónà Uromi sí Obajana nígbà táwọn fijilanté ìlú Uromi dá wọn dúró láti ṣe àyẹ̀wò ọkọ̀ wọn.
Awọn ọmọ ile aṣoju-ṣofin n gbero lati ṣe ayipada abala 131 ati 177 ninu iwe ofin orilẹede Naijiria eyi to sọ nipa ọjọ ori ti ẹni to ba fẹ dije fun ipo gomina tabi ipo aarẹ ni Naijiria gbọdọ to.
Amòfin Effiong sọ pé ilé ẹjọ́ Sharia àti ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Sharia nìkan ni òfin Nàìjíríà fi ààyè gba báyìí tí wọ́n sì ń ṣiṣẹ́ láwọn ìpínlẹ̀ tí wọ́n ti ń lò wọ́n.
Nínú fídíò kan tí Taye Currency fi sójú òpó Facebook rẹ̀ tó sì ti gba orí ayélujára ṣàfihàn rẹ̀ pé àwọn àgbà olórin náà pàdé ní ìlú Saudi Arabia níbi tí wọ́n ti lọ ṣe Umurah ọdún yìí.
Olu ileeṣẹ orilẹede Russia to wà ni Egypt salaye ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Facebook rẹ pe ero marundinlaadọta lo wa ninu ọkọ oju omi naa táwọn ọmọde si wa ninu wọn pẹlu.
Irufẹ iṣẹlẹ yii tun waye lọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu Kẹta yii lasiko ti ijokoo igbimọ ile lori ẹsun iyọnilẹnu fun ibalopọ ti Sẹnẹtọ Natasha Akpoti-Uduaghan fi kan Akpabio n lọ lọwọ.
Ṣáájú àsìkò yìí, onírúurú àwọn ìgbàgbọ́ ló wà nípa iye ìgbà tó yẹ kí èèyàn yàgbẹ́ lójúmọ́ tàbí lọ́sẹ̀ àmọ́ ìwádìí àwọn onímọ̀ bíi Ken Heaton, onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó ní Bristol Royal Infirmary, UK ṣàfihàn pé iye ìgbà tí èèyàn ple yàgbẹ́ yàtọ̀ síra.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo ti BBC Yoruba ṣe pẹlu olukọ naa, Ọgbẹni Ezekiel Olagunju, lo ti sọ pe ko si aṣiri meji ninu ibaṣepọ oun pẹlu awọn akẹkọọ naa, ju pe oun mu wọn gẹgẹ bi ọmọ.