Ẹgbẹ agbabọlu agba orilẹede yii yo koju ẹgbẹ agbabọlu lati orilẹede Guinea Bissau lati mo ẹniti yo bori lati kopa ninu idije ife ẹye adulawọ ni ilu Abuja lọjọ ẹti.
Bi awn mususlumi se bẹrẹ́= aawẹ Ramadan ni ọjọ Satide, ọjọ Keji osu kẹrin ọdun 2022, BBC Yoruba se akojọpọ awọn nnkan to yẹ ki mọ nipa awẹ Ramdan to bẹrẹ.
Awọn awuyeye kọkan tẹle abajade esi idibo naa nibiti ẹgbe oselu mẹta ti woọ Bola Ahmed Tinubu lo ile ẹjọ,ẹgbẹ oselu mẹtẹta na ni ẹgbẹ oselu Labour,PDP ati ẹgbẹ oselu AA.
Nkan miran to ya oun lẹnu ni bi awọn eeyan ti nifẹ ara wọn yatọ si ọgba ẹwọn,oni ọyaya awọn olutaja wu oun lori yatọ si bi awọn ẹlẹwọn ṣe ma u n rọju koko ninu ọgba ẹwọn.
BBC Yorùbá bá ọmọ ìyá méjì tó jẹ́ ọmọ òrukàn sọ̀rọ̀ lórí ọ̀nà tí wọn ń gbà fi ọ̀rá àti ike ṣe epo bẹntiróòlù, tó ń mú owó wọlé àti ohun tó gbé wọn dé ìdí rẹ̀.
Alamojuto eto idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Eko, to tun jẹ giwa fasiti ìmọ ẹrọ FUTA nilu Akurẹ, Ọjọgbọn Adenike Temidayo Oladiji lo kede esi ibo naa ninu eyi to ti sọ pe, ibo 762134 lo gbe Gomina Sanwo-Olu wọle fun saa keji ni iṣejọba.
Fun oͅdun marun un bayii ni awoͅn agbeͅjoͅro ni ilu New York ti beͅreͅ si ni sͅewadii eͅsun pe Trump san owo goͅboͅi fun osere olowonoͅoͅbi teͅleͅ, Stormy Daniels saaju idibo sipo aareͅ oͅdun 2016.
Lára àwọn òfin tí ààrẹ Muhammadu Buhari ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lu náà ni fífi ààyè gba ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ àti ètò ìdájọ́ láti máa ṣe àkóso owó wọn fúnra wọn láì sí lábẹ́ àwọn gómìnà mọ́.
Ọlawalẹ Ṣadare ba BBC Yoruba sọ, o ṣe alaye wi pe ọfisi ti ẹgbẹ naa n lo ni Iyana Kootu ni tosi ile tuntun ni ijọba ibilẹ Ila Oorun-Guusu ni awọn ọmọ ẹgbẹ wọn korajọpọ..
Ileẹjọ fi ẹsun kan Putin pe oun lo sokunfa bi ogun se waye ati bi wọn se fi tipatipa ko awọn ọmọ kekere ni ọna to lodi si ofin lati orilẹede Ukraine lọ orilẹede Russia.
DSS ni awọn afurasi naa n pin akasilẹ fidio kan lori ayelujara, ninu eyi ti wọn ti n pe awọn ololufẹ wọn lati kọlu ẹnikẹni to ba dibo tako ẹgbẹ oṣelu wọn.