Ọpọ ẹhonu lo ti jade si bi baalu Díronu ijagun ileeṣẹ ọmọogun oriilẹ ni Naijiria ṣe ju ado oloro si aarin awọn eeyan ileto naa lasiko ti wọn fi n ṣe ajọyọ Maulud Nabiyy lopin ọsẹ to kọja.
Àtẹ̀jáde tí Agbẹnusọ So-Safe, Moruf Yusuf fi léde ni wọ́n ti fi ìkéde náà síta pé ọ̀gá àgbà àjọ náà, Soji Ganzallo ti buwọ́lù ú pé kí wọ́n lé Adeboye Yusuf Sunday kúrò lẹ́nu iṣẹ́ ọ̀hún.
Abiodun ni inu ibanuje àti iporuru ọkan ni òun àti àwọn ọmọ igbimo ìṣàkóso ipinle Ogun wa láti ìgbà tí ìròyìn ikú Ogbeni Taiwo oyekanmi tí to òun létí.
Ajọ naa wi pe gbogbo eniyan to ba nifẹ si rira baaluu naa ni awọn pe ko fiwe ṣọwọ si wọn ni ibamu pẹlu ofin tita ati rira ẹru fun ileeṣẹ ati ijọba ti ọdun 2007.
Awọn oniṣowo pataki kọọkan kaakiri agbaye, awọn ileeṣẹ to lorukọ, awọn ileetaja, ọdọ, akọroyin ati ajafẹtọ lo lee wa nibẹ, bo tilẹ jẹ pe o loju ibi ti onikaluku ti lee kopa
Ọrọ naa lo waye lẹyin ti awakọ kan, Oyiga Micheal sọ lori ayelujara pe awọn ọlọpaa mu oun lagbagbe Ijesha, niluu Eko lori ẹsun pe oun n lo ẹrọ Google Map naa.
olori ileeṣe ọlọpaa lagbegbe naa, Brig Gen Allan Nobleza ni ẹgbẹ awọn Musulumi kan, Daulah Islamiyah-Maute Group ni awọn fura si pe o ṣeeṣe ko lọwọ ninu ikọlu naa.
Oluṣakoso ọọfisi ijọba ilẹ Amẹrika ni Naijiria, Ọgbẹni David Greene lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu ileeṣẹ iroyin News Agency of Nigeria, NAN, niluu Abuja.
Ọwọ NDLEA tun tẹ arakunrin kan ẹni ọdun mẹrindinlọgọta, Okechukwu Ogala to jẹ baba isalẹ to maa n ko awọn ọdọ lati fi ṣe fayawọ oogun oloro lọ si awọn orileede ilẹ Asia.
Ṣaaju ni banki apapọ ti kede lọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹwaa ọdun 2022, pe oun yoo paarọ awọn owo naa si tuntun, opin yoo si de ba nina tatijọ lọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kejila ọdun 2023 yii.
Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC sọ pe awọn iwa jibiti yii maa n waye ti ọwọ awọn kọlọrọsi ẹda naa ba ti tẹ kaadi ATM eeyan.