Our Services



News From The BBC

A Yoruba Perspective


Ilé ẹjọ́ UK ní Ike Ekweremadu àti ìyàwó rẹ̀ jẹ̀bi ẹ̀sùn kátàkárà ẹ̀yà ara ẹni ọdún 21

Wo irú ìyà tí ìjọba UK, US fẹ́ fi jẹ àwọn ọmọ Nàìjíríà tó fa rògbòdìyàn lásìkò ìbò
Orilẹede mejeeji ninu atẹjade ọtọtọ ni awọn setan fi ofin de iwe irina ẹnikẹni ti wọn ba kẹfin pe o lọwọ ninu bi rogbodiyan se bẹrẹ silẹ lasiko ibo.

Kí ìbò tó dé ni èmi àti Makinde ti ń sọ̀rọ̀, kò sí ìjà mọ́ láàrín wa - Olopoeyan
BBC Yoruba ṣe abẹwo si Ọlọpọeyan fun ifọrọwerọ lori aworan yii ati ede aiyede to waye laarin oun ati Makinde.

Wó àwọn àgbábọ́ọ̀lù Super Eagles tì yóò kojú Guinea Bissau lọ́la
Ẹgbẹ agbabọlu agba orilẹede yii yo koju ẹgbẹ agbabọlu lati orilẹede Guinea Bissau lati mo ẹniti yo bori lati kopa ninu idije ife ẹye adulawọ ni ilu Abuja lọjọ ẹti.

Fídíò tú àṣírí bí ọlọ́pàá Amẹ́ríkà àti òṣìṣẹ iléèwòsàn 10 ṣe fi tipátipá mú ọkùnrin yìí mọ́lẹ̀ títí tó fi kú
Isẹlẹ naaa lo waye ni ọjọ kẹfa osun yii,ti awọn mẹwa to jẹbi ẹsun na ti foju ba ile ẹjọ fun ẹsun to nise pẹlu isekupani.

Ààwẹ̀ Mùsùlùmí bẹ̀rẹ̀ lónìí, Sultan ti Sokoto kédè!

Àwọn adigunjalè ṣèkọlù sí ilé adẹ́rìínpòṣónú, Woli Agba n'Ibadan
Ajewole lo kede isẹlẹ naa lori opo ayelujara rẹ, to si n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun bi o se oun ati idile rẹ yọ ninu awọn adigunjale ewu.

Abia bọ́ sábẹ́ àkóso LP, Alex Otti di gómìnà tuntun; Wo àwọn olùdíje tó borí káàkiri Nàìjíríà
BBC Yoruba se akojọpọ awọn ipinlẹ ti INEC ti kede ẹni to bori esi idibo ati awọn ipinlẹ ti wọn ti kede idaduro ikede esi ibo.

'Ramadan wà láti "charge" wa ni, fáìlì ẹlòmíì ti gaa fún ọ̀pọ̀ ẹ̀ṣẹ̀, bátíìrì wọ́n ti jò'

Èmi ò fi ìgbà kankan tojúbọ ìdìbò ọdún 2023 - Buhari

Mọ̀ nípa ìlànà èlé tuntun tóo bá fẹ́ ya owó bánkì, nǹkan míràn tí CBN kéde lẹ́ka ìṣúná ní Nàìjíríà

Ramadan 2023: Àwẹ Ramadan wọlé dé! Wo nkan márùn-ún tó yẹ kó mọ̀ nípa oṣù ọlọ́rẹ
Bi awn mususlumi se bẹrẹ́= aawẹ Ramadan ni ọjọ Satide, ọjọ Keji osu kẹrin ọdun 2022, BBC Yoruba se akojọpọ awọn nnkan to yẹ ki mọ nipa awẹ Ramdan to bẹrẹ.

Wo àpapọ̀ àwọn tó ti wọ́ Tinubu lọ ilẹ ẹjọ́ lọrí èsì ìbò Ààrẹ
Awọn awuyeye kọkan tẹle abajade esi idibo naa nibiti ẹgbe oselu mẹta ti woọ Bola Ahmed Tinubu lo ile ẹjọ,ẹgbẹ oselu mẹtẹta na ni ẹgbẹ oselu Labour,PDP ati ẹgbẹ oselu AA.

Ní ìbálòpọ̀ akọ sí akọ tàbí abo sí abo kóo fi ẹ̀wọ̀n gbére jura – Ìjọba
Ajafẹtọ ọmọniyan kan nilẹ naa sọ funBBC pe ofin ọhun ti mu ki awọn eeyan maa ṣakọlu si awọn to n ni irufẹ ibalopọ bẹẹ.

Oluwo sọ ọmọ tuntun rẹ̀ ní orúkọ ńlá kan, ẹ wà tú u wò, ẹ wo orùkọ́ aràmàǹdà!

Peter Obi wọ́ Tinubu lọ ilé ẹjọ́, ó ní kí INEC gba ìwé ẹ̀rí mo yege lọ́wọ́ rẹ̀ fún òun
Yatọ si Obi, ẹgbẹ oṣelu Allied Peoples Movement ati Action Alliance naa tun pe ẹjọ.

Gbogbo nǹkan ló ní Àkókò - Davido wú ọ̀rọ̀ síta nípa ìṣẹ̀lẹ̀ aburú tó já lù ú
Ti a ko ba gba lọdun to kọja ni Davido ati afẹṣọna rẹ ti padanu ọmọ wọn ọkunrin, Ifeanyi Adeleke

Atiku wọ́ Tinubu lọ sí ilé ẹjọ́, Ó ní ìbò tó gbé e wọlé kò lẹ́sẹ̀ ńlẹ̀

Wọ́n ti fohùn ráńṣẹ́ ṣáájú pé “ṣóò ní padà wálé torí a máa “disgrace ẹ”, àmọ́ àṣírí wọn rèé – Jandor PDP

Ẹ̀wọ̀n ọdún 241 ní wọ́n jù mí sí, lẹ́yìn tí mo lo ọdún 27, mo fojú rí fóònù, haà! Bí mo ṣe ṣe rèé - Bobby
Nkan miran to ya oun lẹnu ni bi awọn eeyan ti nifẹ ara wọn yatọ si ọgba ẹwọn,oni ọyaya awọn olutaja wu oun lori yatọ si bi awọn ẹlẹwọn ṣe ma u n rọju koko ninu ọgba ẹwọn.

Ìyá àgbà dáná sun ọmọ ara rẹ̀ ọkùnrin, ìyàwó àtawọn ọmọ wọn méjì mọ́lé l’Ondo
Iya agba naa, Iforiti Oloro, n gbe pẹlu ọmọ rẹ ọhun ati ẹbi rẹ niluu Aponmu, to wa lopona ilu Akure si Ondo.

2023 election: Àwọn obìnrin tó wọlé sílé ìgbìmọ̀ aṣòfin ní Kwara, Ondo, àti Ekiti rèé
BBC ṣe akojọpọ awọn obinrin to yege ninu idibo sipo aṣofin ipinlẹ ni Ondo, Ekiti ati Kwara.

Teni entertainer: Idi ti mi ò kì ń ṣí ìhòhò mi bi àwọn olórin obìnrin míran
Ọ̀pọ̀ àwọn ọlólùfẹ́ Teni lórí àtẹjiṣẹ́ twitter lo ti n yin Tẹ́ni pàápàá jùlọ lóri ìmúra rẹ lásikò àjọ̀dún orin tó ṣe tán.

Gómìnà mi ọ̀wọ́n, Ọlọ́rùn yóò mú ọ ṣàṣeyọrí – Ladoja kí Makinde kú oríire
Teslim Folarin to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu APC lo jawe olubori ninu ijọba ibilẹ meji, Orelope ati Irepodun.

'Gbogbo ìlérí tí Sanwoolu àti Hamzat ṣe pátápátá ni wọ́n mú ṣẹ l’Eko' - Ṣé lóòtọ́ ni?

Ẹ wo bí ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù U20 Naijiria ṣe fọwọ́ rẹ́ orílẹ̀èdè Tunisia nímú níbi ìdíje ẹlẹ́kùnjẹ̀kùn Áfríkà
Ẹgbẹ agbabọọlu ti ọjọ ori wọn koi to ogun ọdun (U20 ) ni orilẹ-ede yii gba goolu mẹrin wọ awọn ikọ agbaboolu ti orilẹ-ede Tunisia.

Ọjọ́ méjìlá lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ ìlẹ̀ rìrì Turkey, bí wọ́n ṣe rí òkú àgbàbọọlu Ghana Christian Atsu
Lati ọjọ kẹfa oṣu keji ọdun yi ni Atsu ti di awati lẹyin iṣẹlẹ ilẹ riri nibi ti ile rẹ ti dawo ni agbegebe Antakya, Hatay.

Man city lulẹ̀, Pep Gardiola, Ten Hag jiyàn lórí ‘Offside’ Rashford tó mú góòlù tó sọ Man Utd jí jáde

Agbábọ́ọ̀lù Zambia tẹ́lẹ̀ pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ sọ́wọ́ ajá rẹ̀ mẹ́ta
Ninu atẹjade ti wọn fi lede, Mulala, ẹni ọgọta ọdun ni awọn aja rẹ mẹta ṣekupa lọjọ keje oṣu kinni ọdun ni dede ago mẹta ọsan.

Brazil ṣẹ̀yẹ ìkẹyìn fún akọni agbábọ́ọ̀lù, Pele bó ṣe wọ káà ilẹ̀ sùn
Pele's burial: Wo àwọn ètò ti FIFA àti gbogbo agbéyé là kálẹ̀ nípa ìsìnkú Pele

Wo ìgbésí ayé Pele láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ pẹ̀lú àwòrán
Àwọn àwòrán yìí ṣàfihàn ìgbé ayé Pele.

Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ máleègbàgbé tó ṣẹlẹ̀ lágbo erè ìdárayá Nàìjíríà lọ́dún 2022
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria ni o nifẹ si ere idaraya ati pe wọn fẹran lati ri awọn ọmọ orilẹede yii yege ninu awọn ere idaraya ti wọn kopa ninu rẹ.

Rukayat Motunrayo Shittu: Àwọn ìdí tí ìpò yìí fi tọ́ sí Rukayat nìyí
Rukayat Motunrayo Shittu tó ń díje dupò aṣojù láti Manyan nijọba ibile Asa ni Kwara.ṣàlàyè ohun tó ni lọ́kàn tó fi gbé igba ibò.

Brt-Train Accident: Grandma Oreoluwa ní ìlá alásepọ̀ ló ní òun máà se fún òun tó bá dé
BBC Yorùbá dé ilé Oreoluwa Aina, àgùnbánirọ̀ tó kú nínú ìjàmbá bọ́ọ̀sì BRT àti rélùwéè l‘Eko, táwọn ẹbí rẹ̀ sì sọ irú ẹni tó jẹ́ fún wa.

Adedapo Tejuosho: Olóyè tó bá dán ìdánkúùdán wò lára òkú mi yóò gba Ọlọ́run lọ́gàá
BBC Yorùbá bá Osile ti Oke-Ona Ẹgba, Ọba Adedapo Tejuosho sọ̀rọ̀ nípa ipò tí Nàíjíríà wà àti ọ̀rọ̀ ilẹ̀ Yorùbá.

Plastic to Petrol: Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé ọ̀rá àti ike tí ò ń sọ dànù le mú owó gọbọi wálé fún ọ?
BBC Yorùbá bá ọmọ ìyá méjì tó jẹ́ ọmọ òrukàn sọ̀rọ̀ lórí ọ̀nà tí wọn ń gbà fi ọ̀rá àti ike ṣe epo bẹntiróòlù, tó ń mú owó wọlé àti ohun tó gbé wọn dé ìdí rẹ̀.

Ẹ̀ ń pariwo pé Igbo ni ìyá Gbadebo-Vivour, Ìyá Seyi ọmọ Tinubu n kọ́? Ẹ wá gbọ́ ìtàn - Bode George

Ìdìbò ààrẹ ti ọdún yìí ló burú jù táà ti rí ní Nàìjíríà, ìdí sì ni pé ... - Alága PDP Ogun

Dodo Farms: Ẹ wo bí àwọn ọmọ Yoruba ṣe làlùyọ nídìí iṣẹ́ àgbẹ̀ ní Amerika
Ọpọ ọmọ orilẹ-ede Naijiria lo ti fi ilẹ yii silẹ fo fẹrẹ roke okun ni ilepa ilẹ to lọọra.

Egungun Festival: Ẹ wo bí wọ́n ṣe ń ṣe ọdún eégún ní ìlú Benin Republic
Awọn ara ilu Iyoko ni orilẹede Benin Republic ti tuyaya jade lati ṣe ọdun kan gboogi to wọpọ laarin wọn, iyẹn ọdun egungun.

2023 Elections: Àwọn nǹkan tí o gbọ́dọ̀ mọ̀ kí o tó lọ sí ibùdó ìdìbò nìyí
Àlàyé lórí àwọn nǹkan tí ènìyàn le ṣe ní ibùdó ìdíbò lásìkò ìbò ọdún 2023.

2023 Nigeria Election: Ìgbàgbọ́ wa ní pé Nàìjíríà ṣì máa dùn lẹ́yìn ìdìbò ọ̀la yìí- Àwon olùgbé Nàìjíríà
'Change' yii lagbara fun wa ṣùgbọn síbẹ a maa dibo nitori pe iya yioi to gẹ ni ọrọ awọn ọmọ Naijiria laarọ yii.

Láyé! Mi ò ní pe Sanwo-Olu láti kíi kú oríire, irọ́ ni ìbò tó gbé e wọlé - Gbadebo Rhodes-Vivour
Ó ní òun kọ gbogbo èsì ìbò àti àgbékalẹ̀ ètò ìdìbò tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Eko nítorí ètò ìdìbò náà kò gbé oúnjẹ fẹ́gbẹ́ gba àwo bọ̀.

Funke Akindele sọ̀rọ̀ sókè lẹ́yìn tí èsì ìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Eko jáde
Ninu atẹjade kan loju opo Twitter ati Instagram rẹ lo ti fi ẹmi imoore naa han.

Ẹ wo ibi tí ìjà alágbára méjì tó ń darí Kano yọrí sí; Ànfàní wo ni gómìnà tuntun yìí yóò mú wá?

Nigeria governorship election result: Wo àkọsílẹ̀ iye ìbò tí gómìnà Sanwoolu, Makinde, Dapo àti Abdulrazaq gbà
Tóo ó bá fẹ́ mọ èsì ìbò gómínà tí INEC kéde ní Eko, Oyo, Ogun àti Kwara pẹ̀lú yíká Nàíjíríà, wo Máàpù ìsàlẹ̀ yìí.

Babajide Sanwoolu: Ta ní gómìnà tó tún gba ọpa àṣẹ padà láti tukọ̀ Eko
Sanwo Olu bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ṣíṣe ní ilé ìfowópamọ́ Lead Merchant Bank láàrin ọdún 1994 sí 1997 gẹ́gẹ́ bíì akápò.

Gbajúmọ̀ olórin "Dadakuada", Alhaji Jaigbade Alao jáde láyé!
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ Ajé, ogúnjọ́ oṣù Kẹta ní Ọba orin Dàdàkúàdá náà kí dúnnìyàn pé ó dìgbà ní ìlú Ilorin, olú ìlú ìpínlẹ̀ Kwara.

Dapo Abiodun fìdí Ladi Adebutu àti Biyi Otegbeye janlẹ̀, ó wọlé sáà kejì

AbdulRahman AbdulRazaq borí ìbò, wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kwara

Sanwo-Olu borí ìdìbò gómìnà l'Eko, LP ní àfi kí INEC wọ́gilé ìdìbò ọ̀hún
Alamojuto eto idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Eko, to tun jẹ giwa fasiti ìmọ ẹrọ FUTA nilu Akurẹ, Ọjọgbọn Adenike Temidayo Oladiji lo kede esi ibo naa ninu eyi to ti sọ pe, ibo 762134 lo gbe Gomina Sanwo-Olu wọle fun saa keji ni iṣejọba.

Wo ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà kejì tó wọlé fún sáà kejì l‘Oyo
Bí INEC ṣe kéde Seyi Makinde pé ó wọlé gómìnà fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Oyo, BBC Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ ìtàn ìgbé ayé rẹ̀.

Remi Surutu kí èpè bọnú lórí ọ̀rọ̀ ọmọ rẹ̀ tó dolóògbé, ìdí rèé

Agbébọn ya bo àgọ́ ìdìbò l‘Eko, jí àpótí ìbò gbé, ẹ̀mí kan bọ́, díẹ̀ farapa
BBC Yorùbá lọ yíká àwọn àgọ́ ìdìbò tó wà ní ìpínlẹ̀ Eko, àkójọpọ̀ àwọn ìwà jàgídí-jàgan tó wáyé ní ìpínlẹ̀ náà rèé.

Àwọn ọ̀nà láti fi dá ìròyìn òfégè mọ̀ lásìkò ìbò 2023 nìyí
Awoͅn fidio kan wa lori ayelujara to jeͅ peͅ ti idibo to ti koͅja seͅyin ni, amoͅ ti awoͅn eniyan gbe jade geͅgeͅ bi ohun to waye ni Naijiria.

Mò ń retí kí wóͅͅn wá fi pańpéͅ Ọba mú mi ní Oͅjóͅ Ìsͅéͅgun – Donald Trump
Fun oͅdun marun un bayii ni awoͅn agbeͅjoͅro ni ilu New York ti beͅreͅ si ni sͅewadii eͅsun pe Trump san owo goͅboͅi fun osere olowonoͅoͅbi teͅleͅ, Stormy Daniels saaju idibo sipo aareͅ oͅdun 2016.

Igbákejì Gómìnà tẹ́lẹ̀ ní Ekiti, Bisi Egbeyemi, jáde láyé
Oͅdun 2022 lo kuro ni ipo geͅgeͅ bi igbakeji gomina amoͅ o jeͅ Oͅloͅrun ni ipe ni oͅjoͅ Satide, ọjọ kejidinlogun, osu keͅta, oͅdun 2023.

Wo kókó àyípadà 16 tí Buhari ṣe sí ìwé òfin Nàìjíríà lẹ́sẹẹsẹ
Lára àwọn òfin tí ààrẹ Muhammadu Buhari ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lu náà ni fífi ààyè gba ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ àti ètò ìdájọ́ láti máa ṣe àkóso owó wọn fúnra wọn láì sí lábẹ́ àwọn gómìnà mọ́.

Ọkọ̀ ẹ̀yìn gómìnà Katsina ko ìjàmbá mọ́tò ní ìdìbò ku ọ̀la, èèyàn mẹ́ta kú
Adari eͅka eto iroyin fun gomina ipinleͅ Katsina fi idi isͅeͅleͅ naa muleͅ to si ni oͅloͅpaa meji ati araalu kan lo ku ninu isͅeͅleͅ naa.

Wo Bàbá tó tá ọmọ rẹ oṣù mẹjọ fún òníbara mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
N150,000, N400,000 ati N700,000 ni bàbá tó ta ọmọ rl gbà lọ́wọ́ àwọn èèyàn mẹ́ta tó tà á fún

Wo àwọn ìpínlẹ̀ tó le gbóná àti òpó mẹ́fà tó lé nípa lórí èsì ìbò gómìnà
BBC Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ àwọn ìpínlẹ̀ tó le gbóná lásìkò ìbò ààrẹ àti òpó mẹ́fà tó le nípa lórí èsì ìbò náà.

Gbajúmọ̀ òṣèré tíátà figbe ta pé jàǹdùkú fẹ́ gún òun lọ́bẹ ní àgọ́ ìdìbò
Chioma Akpota figbe ta pé òun ṣe àyẹ̀wò orúkọ àmọ́ tọ́ọ̀gì fi ọ̀bẹ lé òun ní àgọ́ ìdìbò.

Ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti PDP fẹ́sùn kan àràwọn lórí rògbòdìyàn tó gbẹ́mìí èèyàn mẹ́ta n'Ibadan
Ọlawalẹ Ṣadare ba BBC Yoruba sọ, o ṣe alaye wi pe ọfisi ti ẹgbẹ naa n lo ni Iyana Kootu ni tosi ile tuntun ni ijọba ibilẹ Ila Oorun-Guusu ni awọn ọmọ ẹgbẹ wọn korajọpọ..

Iléẹjọ́ ICC pàṣẹ pé kí wọ́n fi Ààrẹ Russia sí àhámọ́
Ileẹjọ fi ẹsun kan Putin pe oun lo sokunfa bi ogun se waye ati bi wọn se fi tipatipa ko awọn ọmọ kekere ni ọna to lodi si ofin lati orilẹede Ukraine lọ orilẹede Russia.

Nigeria Governorship Election: Ọ̀pọ̀ aráàlú fi èrò wọn hàn lórí ìbò gómìnà tí yóò wáyé ní Sátidé
BBC Yorùbá bọ sí ìgboro láti mọ bí ìgbaradì àwọn aráàlú ṣe ń lọ sí lórí ìbò gómìnà tó kò lọ́la àamọ́ èrò wọn ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.

Alfa fipá ṣí ọmọdébìnrin mẹ́rin láṣọ wò nílé kéú, ariwo sọ
Alfa tun fi ipa ba ọmọdebinrin baba yii kan naa, to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlogun lo pọ, ni asiri se tu.

Wo aṣọ àwọ̀sùn tó ń pá ẹ̀fọn táwọn onímọ̀ ṣe síta
Aisan iba jẹ eleyii to wọpọ ni Naijiria to si ti pa ọpọlọpọ eniyan kaakiri ilẹ Afrika ati ni agbaye.

Ọ̀pọ̀ eré tíátà ni mo pàdánù torí ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣe mí lése ní ẹsẹ̀ - Basira Beere
Basira Beere ní ọ̀pọ̀ àwọn olùdarí eré máa ń sọ wí pé òun kò lè kópa nínú àwọn eré kan nítorí ẹsẹ̀ tó ń dun òun.

Báwo ni Oro ṣe fẹ́ dá àjèjì mọ̀, kí ni yóò ṣẹlẹ̀ sí Olóyún tó ń rọbí tàbí aláìsàn lásìkò tí Oro bá jáde ní Eko?
BBC Yorùbá bá Babalawo Idowu Olukunle Adewole, to tun jẹ Akọda Awo sọ̀rọ̀ lórí àwọn ọ̀nà àbáyọ tó wà fáwọn aráàlú láti bọ́ lọ́wọ́ ewu Orò.

Èèyàn 30 ló kù nílé ìwòsàn lára àwọn tó wà níńú bọ́ọ̀sì BRT tó kọlu rélùwéè l'Eko
Kọmiṣọna fun eto ilera ni ipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi ṣalaye bẹẹ loju opo Twitter rẹ lọjọbọ.

Afurasí méjì tó ń fọnrere wàhálà ṣáájú ìbò gómìnà wọ gàù
DSS ni awọn afurasi naa n pin akasilẹ fidio kan lori ayelujara, ninu eyi ti wọn ti n pe awọn ololufẹ wọn lati kọlu ẹnikẹni to ba dibo tako ẹgbẹ oṣelu wọn.

Wo ipò tí IPOB, Boko Haram àti ISWAP wà láàrin agbésùnmọ̀mí àgbáyé
Ikọ agbebon IPOB lo wa ni ipo kẹwa bayii, ti ikọ agbebọn Boko Haram ati ISWAP naa ko si gbẹyin ninu akọsilẹ awọn agbesunmọmi lagbaye.

Wo bí o ṣe lè mọ ibùdó ìdìbò tó yẹ kí o ti dìbò
BBC Yorùbá ṣe àtúpalẹ̀ ìròyìn lórí bó ṣe le rọrùn fún ọ láti mọ àgọ́ ìdìbò rẹ̀ lọ́jọ́ ìdìbò gómìnà àti tàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀.

Ààwẹ̀ gbígbà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ wákàtí lé ṣé àkóbá fún kíndìnrín
Amọran yii wa lati ẹnu Ọga agba fun ajọ naa, Ọjọgbọn Mojisola Adeyeye nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ niluu Abuja.

̀̀́Wo ǹkan mẹfà tí o kò mọ nípa ẹyà Coronavirus tuntun.....
Ẹya arun coronavirus titun tu n ti gbode ti o sii ń tete tan kalẹ ni ilu Amẹrika,ilu Ọba na ti kẹfin ẹya coronavirus titun naa.

COVID-19, Ẹ fọkàn balẹ̀ ìjọba Nàìjíríà kò ni jẹ́ kí Coronavirus tàn kálẹ́ rára- Minisita ìlera
 Minisita fun Ilera, Dokita Osagie Ehanire ti ṣalaye pe Ijọba apapọ n sa gbogbo agbara rẹ lati dena itankalẹ  aarun COVID-19 tuntun.

"Ẹ̀fọn àbaàdì tó ń fa ibà ní Asia ti ń yawọ ilẹ̀ Adúláwọ̀"
Itankalẹ awọn ẹfọn abaadi yii si ni wọn lo n mu ki aayan awọn onisẹ iwadii lati palẹ wọn mọ nilẹ nira si.

O parí! Joe Biden ní Covid-19 dohun ìgbàgbé l‘Amẹ́ríkà ṣùgbọ́n...
Ikede aarẹ yii n waye tohun ti bi iye awọn to n padamu ẹmi wọn lọwọ Covid-19 ṣe n pọ si ni Amẹrika.

Ìjọba ya èèyàn 100 sọ́tọ̀ ní Ghana tórí àrùn pọ̀jẹ̀-pọ̀jẹ̀ Marburg
Isẹlẹ iba pọjẹ-pọjẹ to bẹ silẹ ni Ghana yii ni isẹlẹ keji ti yoo waye lẹyin ti Guinea, lawọn orilẹede to wa lẹkun iwọ oorun Afirika.

Europe Heatwave: London wà lára ìlú tó móoru jùlọ lágbàyéé lónìí, kódà ó gbóná ju Caribbean lọ
Awọn onimọ nipa bi oju ọjọ se ri ti wa kede pe ooru pupọ yoo wa ni UK, France, Spain, Greece àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.

WHO kéde ìkìlọ pàjáwìrì jakèjadò àgbáyé lórí ààrùn Monkey Pox
Monkeypox jẹ aarun ti kokoro aifojuri monkeypox le sokunfa rẹ.O yatọ si kokoro aifojuri smallpox sugbọn oun ko buru to arun igbona 'smallpox'.

Ẹ ṣọ́ra, Monkeypox tún lè dàbí àjàkálẹ̀ ààrùn bíi Coronavirus ní àgbáyé - WHO

Marburg Virus: Ìlànilọ́yẹ̀ rèé láti dènà àrùn pọ̀jẹ̀pọ̀jẹ̀ tó gbòde ní àgbàyé
Ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO ni kokoro arun Marburg ko ṣe wo loju rara nitori bi o ti maa n ṣọṣẹ.

HUMILITASCharleans' Contribution Worldwide

300

Charlean Doctors

250

Charlean Engineers

150

Charlean Lawyers

109

Charlean Professors

We always perform at our best when we work together

Our mission is to provide the means & technical know-how to accomplish the aforementioned with HUMILITAS - always