We Are The Charleans

International News - A Yoruba Perspective

From BBC


Ṣé Donald Trump le ṣe ààrẹ Amẹ́ríkà fún sáà Kẹta?
Donald Trump ní ọ̀pọ̀ èèyàn ń fẹ́ kí òun ṣe sáà kẹta, táwọn alátìlẹyìn rẹ̀ sì ń sọ pé ọ̀nà wà láti gbé e gbà.

Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri Nàìjíríà

Wo àwọn ànfàní tí wíwà nínú oòrùn ń ṣe fún àgọ́ ara
Jijoko sinu oorun lati ma gba oorun naa sara le ṣe agọ ara loore pupọ.

Ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ lórí ìwọ́de láti yọ ààrẹ ilẹ̀ Zimbabwe torí pé ìlú le
Ọpọ ọmọ ilẹ Zimbabwe joko sile dipo ki wọn bọ soju popo lati se iwọde tori bi awọn agbofinro, ti oju wọn ko rẹrin, se lu igboro pa.

Ìjọba Kano lahùn lórí ohun tó fẹ́ kí ìjọba Edo ṣe nípa ọdẹ 16 táwọn èèyàn Uromi dáná sun lásìkò tí wọn ń bọ̀ fọ́dún Ìtúnu Ààwẹ̀
Ní ọ̀sẹ̀ tó kọjá ni àwọn ọdẹ kan tí wọ́n ń ṣe ìrìnàjò lọ sí ìpínlẹ̀ Kano láti ìpínlẹ̀ Rivers lọ ṣọdún ìtúnu ààwẹ̀ ko àgbákò ikú lẹ́yìn táwọn fijilanté ìlú Uromi dáná sun wọ́n fẹ́sùn pé ajínigbé ni wọ́n.

Kí ló kàn lẹ́yìn Ààwẹ̀ Ramadan, ààwẹ̀ Shawwal mẹ́fà ni àbí sísan ààwẹ̀ tí o dín padà?
Ero awọn aafaa ṣọtọọtọ lori eyi to yẹ ko ṣaaju ninu gbigba aawẹ Ramadan ti a din pada tabi gbigba aawẹ Shawwal to jẹ mẹfa.

Bí ọjọ́ ẹ̀tàn, April Fool's Day' se bẹ̀rẹ̀ rèé
Ọjọ́ Kíní, Oṣù Kẹ́rin, ọdọọdún ni àyájọ́ Ọjọ́ 'April Fool' tí àwọn ènìyàn tí máa ń tan àwọn ẹlòmíràn jẹ.

Ladoja lahùn lórí ìkéde ìlú ò fararọ ní Rivers tí ààrẹ Tinubu kéde, gba Wike àti Fubara ní ìmọ̀ràn
Sẹnẹtọ Rashidi Ladoja lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nile rẹ niluu Ibadan sọ ero rẹ nipa ikede ilu o fararọ ni Rivers ti aarẹ Tinubu kede rẹ.

Ọrọ̀-ajé ti fẹsẹ̀ múlẹ̀ l‘Oyo, N12bn la fi ń sanwó oṣù òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀, N10bn fún òṣìṣẹ́ ìbílẹ̀ lóṣooṣù - Makinde
Gomina Seyi Makinde ni idagbasoke ati ọrọ aje ipinlẹ Oyo to fẹsẹ mulẹ ko ṣẹyin ibagbepọ alaafia pẹlu iṣọkan to wa laarin awọn araalu.

Ohun méje tó mú ilẹ̀ ríri ní Myanmar fa ikú rẹpẹtẹ tó lé ní 1,700
Awọn aworan to n jade n ṣafihan bi ọpọ ile ṣe ti bajẹ pẹlu awọn ọna, ni olu ilu Thai, Bangkok ni ile alaja ọgbọn (30-storey) ti wọn n kọ lọwọ ti wo lulẹ.

BBC tú àṣírí gbájúẹ̀ tó ń gba owó lọ́wọ́ ọmọ Nàíjíría fún ìpèsè iṣẹ́ ní UK
Lára àwọn èèyàn tó ń lu jìbìtì náà ni dókítà ọmọ Nàìjíríà kan tó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àjọ ìlera ilẹ̀ UK, NHS ní ẹ̀ka àwọn tó máa ń rí sí ìtọ́jú ààrùn ọpọlọ.

Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ Peller já kúrò lójú òpó TikTok rẹ̀, àwọn kan tún ń dúnkokò láti yìnbọn mọ́ torí ọ̀rọ̀ tó sọ
Peller lórí TikTok tó ṣe sọ pé èèyàn kan dúnkokò mọ́ òun pé wọ́n máa yìnbọn mọ́ òun tí òun bá fi lè kọjá ní agbègbè Lekki Phase 1.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Mó ní òṣìṣẹ́ 42 àmọ́ mò jẹ wọ́n lówó oṣù mẹrin, mò ń la nǹkan kọjá torí ìlú le - Ibrahim Chatta
Ilumọọka oṣere naa ni bi ọrọ-aje Naijiria ṣe dẹnu kọlẹ naa lo fa a toun ko fi ri owo oṣu awọn oṣiṣẹ oun san.

Wọ́n gún ẹ̀ṣọ́ Emir Sanusi ní ọ̀bẹ pa, òmíràn fara gbọgbẹ́ lásìkò tó ń bọ̀ níbi ìrun ọdún Ìtúnu Ààwẹ̀
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ni Kano, Abdullahi Kiyawa, lo sisọ loju isẹlẹ naa lọjọ Aiku nilu Kano.

Díẹ̀ ló kù kí n jáwọ́ nínú dídu ipò ààrẹ lásìkò ọ̀wọ́ńgógó Naira, ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò kọjú re sí mi – Tinubu
Aarẹ Tinubu sọrọ yii lọjọ Abamẹta, lasiko ti awọn eeyan n ṣinu aawẹ ọjọ naa pẹlu rẹ nile agbara to wa l'Abuja.

Mọ̀ nípa àbá òfin tó lè mú ọ ṣ'ẹ̀wọ̀n tàbí san fáìní N100,000 tí o bá kọ̀ látì dìbò
SERAP sọ ninu iwe to kọ si ile aṣofin pe riran awọn ọmọ Naijiria ti wọn ti to ibo di ṣugbọn ti wọn ko dibo lọ sẹwọn, tako alakalẹ to wa ninu iwe ofin Naijiria àti ẹtọ ọmọniyan lagbaaye.

"Ilé tó lé ní igba ni wọ́n jó ní Erin-Osun, ìgbà kejì tí wọn yóò jó ilé mi rèé, n kò ní aṣọ kankan lọ́rùn mọ́"
BBC Yorùbá dé ìlú Ilobu àti Erin Ile níbi tí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá olówó iyebíye ti ṣòfò, ọ̀pọ̀ èèyàn sí ló fi omijé sọ̀rọ̀ nípa àjálù tó bá wọn."

Kókó ọ̀rọ̀ tí Alaafin Oyo tuntun sọ l'ọdun Ìtúnu Àwé lẹ́yìn tó dé Adé Sango tán ní Koso
Alaafin Owoade to gba ade Sango ni Koso lọjọ Abamẹta ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Kẹta niluu Oyo sọrọ yii ninu ọrọ ikini ku ọdun to fi ranṣẹ sawọn musulumi to n ṣe ọdun itunu awẹ.

Abẹ̀sẹ́kùbíòjò ọmọ Nàìjíríà Olanrewaju ṣubú lulẹ̀ lásìkò tó ń jà lọ́wọ́, ó sì jáde láyé
Fidio ija Olanrewaju ati Mbanugu ti a ri lori itakun ayelujara fi idi rẹ mulẹ wi pe oun gan an lo n lewaju pẹlu ami ayo to pọju ninu ija ọhun ki o to ṣubu lulẹ.

Ìjíròrò láti dáwọ́ oogun dúró láàárín Israel àti Hamas tún gbérasọ
Ìgbésẹ̀ ọ̀tun yìí yóò pèsè fún Hamas láti tú àwọn èèyàn Israel márùn-ún tó wà ní àhámọ́ wọn sílẹ̀, tí wọ́n sì máa sinmi oogun fún àádọ́ta ọjọ́.

Ilẹ̀ rírì tó wáyé ní Myanmar ti gbẹ̀mí èèyàn 1,600
Ọ̀pọ̀ àwọn tí ilẹ̀ rírì ṣàkóbá fún ni kò rí ọ̀nà láti àwọn ohun èlò ìrànwọ́ tí wọ́n pèsè fún wọn bí ilẹ̀ rírì náà ṣe ti ba ọ̀pọ̀ ọ̀nà àti ohun améyédẹrùn jẹ́.

Aláàfin Oyo tuntun Ọba Akeem Owoade dé Adé Sango ní Koso, ìlú Oyo mì tìtì
Eyi waye lẹyin ti Kabiyesi Owoade kuro ni Ipebi lọjọ Ẹti ọjọ kejidinlọgbọn oṣu yii nibi ti ori-ade naa ti wa fun bii ọjọ mọkanlelogun.

Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò, dúkìá bàjẹ́ níbi ìjà ilẹ̀ láàrin ìlú Osi àti Epe Opin ní ìpínlẹ̀ Kwara
Laasigbo naa bẹrẹ ni Ọjọbọ ọsẹ yii, eyi to si yọri si iku tẹgbọn taburo ọmọ iya kan naa ti wọn jẹ ọmọbibi ilu Osi.

''Ìgbà tí mo ti jẹ ọba, ni àwọn obìnrin tó fẹ́ ẹ́ fẹ́ mi ti pọ̀ si nítorí ẹwà mi''
Laipẹ yii ni Ọba Olusola Osolo, di gbajugbaja lori ayelujara, deebi pe , wọn fun ni inagijẹ Kabsbaby

Taa ni Aisha Achimugu, gbajúmọ̀ oníṣòwò, tí EFCC kéde pé òun ń wá?
Àtẹ̀jáde kan tí àjọ náà fi sórí ìkànnì ayélujára wọn lọ́jọ́ Ẹtì, ọjọ́ Kejìdínlọ́gbọ̀n, oṣù Kẹta ni wọ́n ti kéde pé àwọn ń wá obìnrin náà fẹ́sùn lílẹ̀dí àpòpọ̀ láti hùwà ọ̀daràn àti kíkó owó ìlú lọ sí ilẹ̀ òkèrè.

Ọ̀rọ̀ ìwúrí tí Florence Ajimobi sọ láyàájọ́ ọjọ́ ìbí ọmọ rẹ Abisola, kó tó ò kú lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì
Iya Bisola ko mọ pe gudugbẹ yoo ja lẹyin ọjọ diẹ to n ki ọmọ rẹ kuu ayẹyẹ ọjọọbi pẹlu ọpọlọpọ adura.

Aráàlú dáná sun àwọn arìnrìnàjò nípìnlẹ̀ Edo, èèyàn méje kú
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́, wọ́n ní àwọn èèyàn tí wọ́n pa ọ̀hún ń ṣe ìrìnàjò lọ ní òpópónà Uromi sí Obajana nígbà táwọn fijilanté ìlú Uromi dá wọn dúró láti ṣe àyẹ̀wò ọkọ̀ wọn.

Aláàfin Oyo tuntun jáde ní Ìpèbí lẹ́yìn ọjọ́ bíì mọ́kànlélógún, ariwo sọ l'Oyo
Ọjọ Ẹti ọjọ keje oṣu Kẹta yii ni kabiyesi Owoade wọ Ipebi.

Mọ̀ nípa àbá òfin ọjọ́ orí olùdíje ààrẹ Nàìjíríà, ìdájọ́ ikú àtàwọn míì tí ilé aṣòfin l'Abuja ń gbé yẹ̀wò
Awọn ọmọ ile aṣoju-ṣofin n gbero lati ṣe ayipada abala 131 ati 177 ninu iwe ofin orilẹede Naijiria eyi to sọ nipa ọjọ ori ti ẹni to ba fẹ dije fun ipo gomina tabi ipo aarẹ ni Naijiria gbọdọ to.

Wo àwọn nǹkaan mẹ́wàá tó yẹ láti ṣe lọ́jọ́ ọdún Eid-el-fitr
Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀sìn Islam ṣe là á kalẹ̀, àwọn mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nǹkan mẹ́wàá yìí lọ́jọ́ ọdún láti mú kí ọdún dùn fún wọn.

Àwọn nǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nipa Abisola, ọmọbìnrin Gómìnà Abiola Ajimobi, tó jáde l'áyé
Laaarọ Ọjọbọ ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu Kẹta yii ni iroyin iku Abisola Kola-Daisi, jade si ori ayelujara.

Makinde yí ẹnu padà lórí ilé-ẹjọ́ Sharia nípìnlẹ̀ Oyo, ó sọ ìhà tó kọ sí i báyìí
MURIC sọ fun BBC Yoruba wi pe ''a o kuku nija pẹlu ijọba, ohun ta n beere naa ni ẹtọ, ki wọn ṣe deede fun Musulumi ati Kristẹni.''

Kò sí ohun tó ń jẹ́ ìgbìmọ̀ Sharia lábẹ́ òfin Nàìjíríà, ohun tí òfin sọ rèé – Amòfin
Amòfin Effiong sọ pé ilé ẹjọ́ Sharia àti ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Sharia nìkan ni òfin Nàìjíríà fi ààyè gba báyìí tí wọ́n sì ń ṣiṣẹ́ láwọn ìpínlẹ̀ tí wọ́n ti ń lò wọ́n.

Àwọn ànfààní tó wà nínú àjọ SWDC tí Tinubu ṣèṣẹ̀ buwọ́lu ìdásílẹ̀ rẹ̀ fún ilẹ̀ Yorùbá
Ajọ SWDC wa fun idagbasoke awọn ipinlẹ ilẹ Yoruba nipa ṣiṣe oniruuru akanṣe iṣẹ kaakiri ẹkun naa.

Ẹbí dáwọ́ lu ìyàwó oníyàwó lálùbami nítorí ó kọ̀ láti bu ìyẹ̀pẹ̀ sí òkú ọkọ rẹ̀ àtijọ́
Iṣẹlẹ naa waye ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹta ọdun 2025.

O wà nínú ewu láti ní oyún ìju, tí ìyá, ẹgbọ́n tàbí àbúrò rẹ bá ní i
Awọn nnkan to n fa oyun iju fun awọn obinrin ni Naijiria ati ọna abayọ





We always perform at our best when we work together

Our mission is to provide the means & technical know-how to accomplish the aforementioned with HUMILITAS - always



This Section Can Accommodate Your Adverts





Charleans In Celebration Mode

We have put an assorted mix of pics here for your enjoyment. We are always hungry for more - so if you have taken or have access to some pics remotely related to our issue, please do not hesitate to send them to the web admin team

SCOBA PARTNERS

corporates and enterprise businesses we have the pleasure to connect with.